Description

Iwẻ yií je àkójopò ese Ifá ti a mú láti inú àwon Ojú Odù (Olojà) Mérèerindinlógún. A mú ese Ifá méjo-méjo láti inů Odù kookan bèrè láti inú Eji Ogbè títi tí ó fi kan Ofün (Oràngún) Méji. lyàtò ti ở wà nínú iwé yii àti àwon iwé Ifá ati ewi àdáyébá miiràn ni pé a se àlàyé ese IfÃ¥ kòòkan tiÅ„ bẹ ninú iwé yii léseese. A se èyí nitori pé ati ÅŸe àkiyèsi wi pé àwon ese Ifá wonyí kii yé àwon akékoo àti olùkó náà dáadáa nigbà tí won bá Å„ kà won. Edè àtayé báyé ni èdè Orúnmilà. Nitorí náa kò ya ‘ni lénu wipé èdè lIfá ki í tètè yé ogbèri. ldi niyí ti a fi se àlàyé sókisókí lóri esÄ™ koökan. Fún eni ti ó bá ni òye ti ó si ní ife si ese Ifä, a lérò pé àlàyé wònyi ó jèe ilànà pàtäki nigbà ti ó baÅ„ ka iwé yii finífini. Ni ibère iwé yii, a se àlàyé nipa ohun ti Ifa je gége bi orisà àti ewi àdáyébá Yorùbá. A lérò wi pé àlàyé yii náà ó ran àwỌn ònkàwé wa lówó láti mo ipò ti Ifá kó ninú ogbá»™n, imò àti iríri omo Yorùbá.

Additional information

book-author

Reviews

There are no reviews yet.

Be the first to review “Awon Oju Odu Meerindinlogun”

Your email address will not be published. Required fields are marked *